Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Kò sí nǹkan tó máa dá ìkọlù wa sí Rafah dúró - Netanyahu
Eyi lo jade lasiko ti igbinyanju pe ki adehun waye pe ki awọn juwọ ogun silẹ, ti wọn si tu awọn eeyan to wa ni ahamọ silẹ.

Mọ ìdí tí CBN fòfin de Opay, Palmpay àtàwọn míì láti yé ṣí akoto owó fáwọn oníbàárà tuntun
Àwọn ilé iṣẹ́ bíi Opay, Kuda Bank, Palmpay àti Moniepoint ni ọ̀rọ̀ náà kàn, tí wọn kò ní ní àǹfàní láti gba àwọn oníbàárà tuntun láàyè láti ṣí akoto owó pẹ̀lú wọn fún ìgbà kan ná.

Àwọn afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pa èèyàn kan, jó ilé ìgbé méjì gbúrúgbúrú ní Kwara
Iroyin ni lalẹ ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 2024 ni rogbodiyan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa ti wọn si faa titi di ọjọ Iṣẹgun.

Kí lẹ ti gbọ́ nípa ọmọ ọdún mẹ́rìnlá tí wọ́n pa ni Hainault ni London?
Yatọ si eyi, Hainault tun wa lara awọn agbegbe ti awọn eeyan n wa julọ lori ikanni ayelujara ti Google lasiko yii.

Kí ló fa gbas-gbos láàrin Davido àti Wizkid lórí ayélujára?
Ori itakun ayelujara X ni rogbodiyan naa ti waye lopin ọsẹ.

Ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ lágbàáyé: Ìdí tí wọ́n fi yan ọjọ́ àkọ́kọ́ oṣù Karùn-ún?
Lẹyin ti Ogun Agbaye akọkọ pari, ti ayipada rere ti n ba awọn oṣiṣẹ, ti idagbasoke ti n de pẹlu iyanju awọn ajafẹtọọ ọmọniyan ni Russia, o dohun ti awọn oṣiṣẹ n beere ohun gbogbo to tọ si wọn kaakiri aye.

Mo ní ìjàmbá ọkọ̀ nígbà mọ́kànlá, mo si ro ará mi pin láyé pé ó ti parí- Adeola Testimony
O ni ọpọ igba ni oun ti pinnu pe oun fẹ gba ẹmi ara oun ki Ọlọrun to gbe kongẹ Iyawo rẹ.

“Lẹ́yìn ọdún kan tí wọ́n fi ipá bá ọmọ mi ọmọ odún mẹ́ta lòpọ̀, mò ń wá ìdájọ́ òdodo”
“Nnkan to ṣẹlẹ si ọmọ mi, mi o fẹ ko ṣẹlẹ si ọmọ ẹlomiran.”

Òjò ńlá àti omíyalé ṣekúpa èèyàn tó lé ní 40
Ojo arọrọda to lagbara lo fa iṣẹlẹ naa, ti o si tun sọ ọpọlọpọ eeyan di alai ni ile lori lẹyin ti Damu to wa ni Kamuchiri ni iwọ oorun Kenya ya.

Ìdá 0.4% péré ló gba máàkì tó lé ní 300 nínú ìdánwò ọdún yìí – JAMB
Oloyede ni “ninu awọn 1,842,464 to ṣe idanwo, ida 24% gba maaki to le ni 200.”

Gómìnà àná Kwara, Abdulfatah Ahmed fojú ba ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ṣíṣe owó ìlú kúmọkùmọ
Abdulfatah Ahmed ti ọpọ mo si Maigida lo n jejọ lori ẹsun sisowo ilu to to billionu mewaa Naira mokumoku ni asiko rẹ gẹgẹ bii gomina ipinlẹ naa laarin ọdun 2011 si 2019.

Ilé-ẹjọ́ pàṣe kí Multichoice dáwọ́ àfikún owó orí DSTV àti Gotv dúró
Ile-ẹjọ sọ pe o digba ti awọn ba pari igbẹjọ naa, ki awọn to le gbe idajọ kalẹ boya DStv yoo ṣafikun tabi gbagbe nipa fifi owo kun owo ori awọn ọja wọn.

"Inú òkùnkùn birimù ni gbogbo Naijria yóò wà lóṣù mẹ́ta sí àsìkò yìí tí a bá kọ̀ láti fikún owó iná"
Ṣugbọn nigba to n fesi, olori igbimọ aṣofin ọhun, Enyinnaya Abaribe, sọ pe iya njẹ awọn araalu lọwọ yii.

Aláboyún àti àwọn mẹ́jọ farapa níbi ìjámba iná gáàsì l’Ékòó
Yatọ si alaboyun to farapa, awọn ọmọ kekeeke ati agbalagba naa fara kaaṣa ijamba yii, bo tilẹ jẹ pe wọn ti wa nibi ti wọn ti n gba itọju lọwọ.

Wo ohun tí àwọn aráàlú ń là kọjá nítorí àìrí epo bẹntiróòlù rà lónìí
Bo tilẹ jẹ pe ajọ NNPCL to n ri si ọrọ epo rọbi sọ lopin ọsẹ wi pe awọn ni epo to to ọmọ Naijiria lo ni ipamọ, alukoro ẹgbẹ IPMAN, Ọgbẹni Chinedu Ukadike ti fidi rẹ mulẹ pe ko si epo to to araalu lo ni Naijiria lọwọ yii.

Bàbá àtọmọ kó sọ́wọ́ ajínigbé ní Ondo, ọlọ́pàá ati iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
Lasiko ti wọn n rinrin àjo lati ipinlẹ Edo lọ si ilu Imeri ni ijọba ibilẹ Ose, nipinlẹ Ondo ni wọn ko sọwọ awọn ajinigbe naa.

Ọ̀wọ́ngógó epo: Ìjọba Kwara bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti fi kélé òfin gbé àwọn alágbàtà tó n gbé epo pamọ́
Igbimọ amuṣẹṣe ti Gomina AbdulRahman AbdulRazaq yan, eyi ti olori awọn oṣiṣẹ gomina, Ọmọọba Mahe Abdulkadir jẹ adari wọn, nigba to n sọrọ, jẹ ko di mimọ pe awọn ko le laju silẹ lati maa jẹ ki awọn elepo fiya jẹ araalu lai nidi.

Ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ Fáṣítì US dèrò àhámọ́ nítorí ìfẹhonúhàn tí wọ́n ṣe lórí ìkọlù Israel sí Gaza
Oludije aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Green Party, Jill Stein naa pẹlu awọn eeyan to wa ni ahamọ Ileeṣẹ ọlọpaa.

Wo àwọn nǹkan méje tí o kò mọ̀ nípa Egbin Orun, akọrin ẹ̀mí tó dolóògbé
Olorin ẹmi bii tiẹ, Esther Igbẹkẹle, lo fi iroyin iku naa soju opo Instagram rẹ lọjọ Satide, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin yii.

'Ìbejì ni wá ṣùgbọ́n àyẹ̀wò DNA ní bàbá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ló bí wa'
Awọn onimọ sayensi ṣalaye pe, iru iṣẹlẹ yii ṣọwọn, ti ko si ju mẹwa lọ to ni akọsilẹ lagbaye ṣugbọn o wọpọ laarin ẹranko.

Oyún oṣù méje ààbọ̀, tí Dókítà gbé jáde nínú ìyá rẹ̀ ní Gaza, ti jáde láyé
Ẹlẹmi gba ẹmi ọmọ jojolo naa ni Ọjọbọ ana, ti wọn si ti sin i si ẹgbẹ iya rẹ ẹni ti wọn fi orukọ rẹ sọ ọ.

Ìwọ́de gbòde ní Australia láti fòpin sí pípa àwọn obìnrin lọ́nà àìtọ́
Olóòtú ìjọba Australia, Anthony Albanese ní ọ̀rọ̀ náà ti di ohun tó ń dààmú gbogbo orílẹ̀ èdè àwọn.

Kí ló dé tí àwọn èèyàn kan ń fi apá jánú lórí ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Ọ̀yọ́?
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) n'ipinlẹ Ọyọ ti fi ọrọ lede wi pe irọ lasan ni pe eto idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ,

Mọ̀ nípa ẹgbẹ́ kan tó wà fún àwọn obìnrin tí kò fẹ́ l'ọ́mọ láyé
Ileeṣẹ BBC ba awọn obinrin to jẹ ọmọ ẹgbẹ Bristol Childfree Women sọrọ, wọn si salaye idi ti wọn ri ti wọn fi pinnu igbesẹ yii.

Wo pàtàkì iṣan tó ń ṣiṣẹ́ bíi ọkàn, mú kí èèyàn fẹsẹ̀ méjì rìn, ó tún ń mú kí ẹ̀jẹ̀ ṣàn lára
Dokita Carles Pedret, akọṣẹmọṣẹ lati ileewe to n ri si ilera nipa ere idaraya ni Yunifasiti Barcelona ni iṣan Soleus nilo lati maa ṣiṣẹ deede keeyan le wa lalaafia ara.

Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ s’áwọn tó fẹ̀hónú hàn nítorì ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní Benin
Nibi ti iwọde ọhun ti n lọ lọwọ lawọn ọlọpaa ti ko mẹtadinlogun (17) ninu awọn oluwọde naa.

Kí ló dé tí wàhálà bẹ̀rẹ̀ bí Togo ṣe fẹ́ kúrò nílànà òṣèlú ààrẹ sí ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn?
Atunṣe iwe ofin ni ọdun 2019 fi aye gba Aarẹ Gnassingbe lati jade dupo, eyi to fun ni anfani lati wa nipo títi wọ ọdun 2030.

Wo ọ̀nà tí o lè gbà borí àìsàn rọpá-rọṣẹ̀ tó ń pa ọ̀gọ̀rọ̀ lágbáyé
Ajọ eto ilẹra ni Naijiria, NMA ti ni o kere tan eniyan 13m lagbaye ni yoo ni aisan rọpa-rọṣẹ lagbaye.

Kí ni El Niño àti La Niña, kí ní àjọṣepọ̀ wọn pẹ̀lú ojú ọjọ́?
El Niño ati La Niña, mejeeji yii jẹ ohun pataki si ayipada oju-ọjọ lagbaye.

Ẹ má kó oúnjẹ 5000 tí mo pín lọ sílé yín, àwọn mẹ̀kúnnù tó nílò rẹ̀ ni kí ẹ pín fún - Sanwo-Olu kìlọ̀
Ijọba Eko ni awọn eeyan ijọba ibilẹ ogun ati tawọn onidagbasoke (LCDA) mẹtadinlogoji to wa l’Ekoo ni yoo janfaani ounjẹ naa.

Local Housing

This is one of the main issues facing local people. The inadequacy of social housing stock continues to be the main concerns of local people. And it is getting worst.

Read More

Drugs And Illegal Substances

Taking illegal drug is always fraught with danger. You don't need me to tell you that - your grand mother will say the same. The high very often tend to perpetual low that you will never get out from. Get advise now before it is too late

Read More

Knife Attacks

Who goes around with a knive as weapon of protection is deluded. It will inevitably be your comeuppance. Just in case you do not understand, it will kill you. There is no justification for carrying a knive excerpt when you are foraging in the jungle.

Read More

Gang Culture

We were all young once - doing things adults will frown upon. This was at school or in the play grounds. But as we grew up, people we wanted to associate with start to shrink in numbers as our brain matured correspondingly and as a result doing the right thing. Pick your friends judiciously.

Read More

Local Parks

From a personal experience - the local park is a refuge for meditation,physical exploration and mental rejuvination. Just go for a slow run and see how you feel afterwards. Physical and mentally rewarding. Don't just take my words for it - it is a scientific fact. Please do try it.

Read More

24/7 Support

We are your one stop local solution advocate. Dont't carry all that weight on your own we are here to not only relief some of it, but to help you get back to you again.

Read More
Established since 2000

We Are Ready To Assist