Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Agbébọn pa olùkọ́, jí ọ̀gá àgbà àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé lọ l'Ogbomoso
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹẹẹdogun oṣu Karun-un ọdun 2026 yii ni awọn agbebọn naa pa olukọ kan, ji olori ile ẹkọ pẹlu awọn akẹkọọ ti ẹnikẹni ko ti i le fi iye wọn mulẹ lọ nibi ikọlu naa.

Kóòtù sọ Blessing CEO sí àhámọ́, fún ẹ̀sùn lílu jìbìtì N36m
Ile ẹjọ giga ilu Eko to wa n'Ikoyi, niwaju Adajọ D.I. Dipeolu ni Blessing to kede pe oun ni arun jẹjẹrẹ laipẹ yii ti farahan.

Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
Lori eto Agbole Akọni BBC News Yoruba, idile Ogboriefon ni ilu Ibadan ni a balẹ si lati mọ nipa bi akọni yii ṣe lo igbesi aye rẹ nigba to wa laye.

Ààrùn Ebola tún gbòde, gbẹ̀mí èèyàn 65
Ajọ Centres for Diseases Control and Prevention ni Africa, CDC sọ pe eeyan 246 ni wọn ti ṣawari rẹ pe o lugbadi aarun naa, ti wọn si ṣe akọọlẹ iku eeyan marundinlaadọrin (65) ni agbegbe Mongwalu ati Rwanpara.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Làásìgbò bẹ́ sílẹ̀ lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC Oyo, wọ́n ba ilé ẹgbẹ́, dúkìá àwọn olùdíje sípò gómìnà jẹ́
Iroyin ni awọn ọmọ ẹgbe oṣelu APC ti inu n bi pẹlu awọn nnkan to n ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ ni wọn lọ sile ẹgbẹ naa ti wọn si lọ da nnkan ru.

Ariwo ayọ̀ ní ààfin Ooni ti Ile Ife bí Olori Mariam ṣe bí ìbejì ọkùnrin
Kabiyesi Arole Oodua fúnra rẹ lo fi ìròyìn náà léde lójú òpó ayélujára Instagram rẹ ní ìdajì oni ọjọ́ Ẹtì.

Ilé ẹjọ́ ju pásítọ̀ sí ẹ̀wọ̀n gbére fún bíbá ọmọdé mẹ́ta lò pọ̀, ó tún ṣẹ́ oyún fún wọn
Olayinka ni olori ijọ Mission House of Divine Land of Joy and Prayer Ministry, nipinlẹ Kwara, lara awọn ọmọ to n wa si ṣọọṣi rẹ ni wọn lo ṣe aṣemaṣe pẹlu.

Gómìnà Seyi Makinde kéde pé òun yóò dupò ààrẹ Naijiria ni 2027
‎Ẹgbẹ oṣelu Allied Peoples' Movement (APM) ni Seyi Makinde ni oun yoo ti dupo aarẹ Naijiria ni 2027.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ bí Trump ṣe ń ṣàbẹ̀wò sí Ààrẹ Xi ní China
Ọdun 2017, nigba to n ṣe saa rẹ akọkọ gẹgẹ bi aarẹ America ni Trump ti ṣe abẹwo bayii gbẹyin si China.

Àwọn ọmọ Nàìjíríà máa fi ojú àwọn olóṣèlú dánrin níbi ètò ìdìbò tó ń bọ̀ - Seyi Makinde
Seyi Makinde ni oun gbagbọ pe awọn ọmọ Naijiria maa dibo fun ẹni to ba wu wọn nibi eto idibo gbogbogbo ọdun 2027 lai fi ẹgbẹ oṣelu ṣe.

Ẹbí Alexx Ekubo sọ̀rọ̀ lórí irúfẹ́ jẹjẹrẹ kíndìnrín tó sokùnfa ikú rẹ̀
Aisan jẹjẹrẹ kindinrin maa n ṣe eeyan nigba ti awọn sẹẹli aisan jẹjẹrẹ ba bẹrẹ si ni pọ ninu kindinrin eeyan.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ajínigbé fi ayédèrú iṣẹ́ tàn mi lọ sí Zamfara, wọ́n tún fowó ọkọ̀ ránṣẹ́ kí n lè tètè wá - Akẹ́kọ̀ọ́jáde Fásitì
Ọna keyeefi ti eeyan ko le rokan rẹ ni awọn ajinigbe naa gba pitu ọwọ wọn fun Arum Azi to kẹkọọ gboye ni Yunifasiti Jos, ipinlẹ Plateau.

Ọ̀pọ̀ èrò n‘Ibadan fẹ̀sùn ajínigbé kan Dókítà kan, wọ́n fẹ́ lú ú pa, dáná sun ọkọ̀ rẹ̀, ọ̀pẹ́ ọlọ́pàá tó dé sásìkò
Dokita naa ti a gbọ gbe o wale lati Amẹrika lawọn eeyan kan sọ fun ileeṣẹ ọlọpaa to wa lagbegbe Eleyele wi pe awọn eeyan kan ti fẹ dana sun lagbegbe Ologuneru.

Wo kókó ohun tó ń ṣẹlẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Labour tí wọn fi ní kí Olóòtú Ìjọba UK kọ̀wé fipò sílẹ̀
Lẹyin ipade ọjọ Iṣẹgun ni Akọwe ilegbee, Steve Reed ati akọwe ijọba fun ọrọ iṣẹ ati owo ifẹyinti, Pat McFadden, sọ pe awọn si wa lẹyin Olootu Ijọba.

Àwọn agbébọn mẹ́ẹ̀dógún ya wọ agboolé táwọn ilégbèé wà ní Ijebu-Ode, jí èèyàn mẹ́ta gbé lọ
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe awọn afurasi agbebọn ti iye wọn fẹ ẹ to mẹẹdogun ni wọn yabo ibugbe Ipojo Golden Estate to w ani agbegbe Oke-Eri ni nnkan bii aago meje irọlẹ pẹlu awọn ohun ija gidi.

Ẹgbẹ́ alákatakítí ISIS, Al Shabaab àti Al Qaeda tí a lé ní Iraq àti Syria, ti fi ìwọ̀ oòrùn Afrika ṣe ibùba – Ìjọba Amẹrika kìlọ̀
Amẹrika ni afojusun oun ni lati ri pe awọn agbesunmọmi to n ṣọṣẹ ni Afrika ko lagbara to lati ṣe ikọlu si oun tabi awọn ti oun ni ibaṣẹpọ pẹlu ni Afrika.

Olùkọ́ fásítì tí wọ́n lù, yẹ̀yẹ́ níta gbangba pé ó ń bá akẹ́kọ̀ọ́ lòpọ̀ ní yàrá ìkàwé, ohun tí a mọ̀ rèé
Koda, iroyin sọ pe Alufaa ijọ Aguda ti a mọ si Katoliiki ni ọkunrin ti wọn n lu ninu fidio naa.

Ìdí rèé tí ẹgbẹ́ òṣèlú NDC fi gbé ipò Ààrẹ sí ìhà gúúsù lọ́dún 2027, Peter Obi ni olùdíje ààrẹ, èmi ni igbákejì rẹ̀ - Kwankwaso
Kwankwaso, ti oun ati Peter Obi fi ẹgbẹ oṣelu ADC silẹ lọ sinu NDC lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ileeṣẹ iroyin Arise.

Lẹ́yìn tí ajínigbé gba N50m owó ìtúsílẹ̀, wọn pa àgbà olóṣèlú lẹ́gbẹ́ ADC, fi òkú rẹ̀ ránṣẹ́
Iroyin ni ọgọrun-un miliọnu naira ni awọn ajinigbe naa kọkọ beere fun gẹgẹ bi owo itusilẹ ki wọn to din owo naa ku si aadọta miliọnu naira.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí ọkọ̀ òfurufú tó ń bọ̀ láti Amẹ́ríkà, tó yẹ kó balẹ̀ l‘Eko padà láì já èrò inú rẹ̀, lẹ́yín tó dúró fún wákàtí mẹ́jọ lójú òfurufú
Iroyin ni awọn ero inu ọkọ ofurufu naa lo ọpọ wakati loju ofurufu ni ọjọ Abamẹta naa to si jẹ pe wọn ni lati pada si ibi ti wọn ti n bọ bii ileeṣẹ ọkọ ofurufu naa ṣe ṣadede wọgile irinajo ọhun lai sọ ohun to ṣẹlẹ ni pato.

Ṣé lóòótọ́ ni àdó olóró tí ológun Chad jù fún Boko Haram pa ọ̀pọ̀ apẹja ọmọ Naijiria?
Ikọlu yii n waye lẹyin ọjọ diẹ ti ikọ agbesunmọmi Boko Haram kọlu ileeṣẹ ologun Chad nigba meji.

Láì ṣe IVF, obìnrin kan bímọ márùn-ún lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo lẹ́yìn tó fi ọdún méjìlá yàgàn
Ohun to jẹ kayeefi ju ninu ọrọ rẹ ni pe Bedriya ko lo ilana iloyun igbalode; 'In Vitro Fertilization' (IVF) to fi loyun awọn ọmọ marun-un yii.

Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì
Akọroyin BBC News Yoruba wa nibi iwọde naa, to si bawọn osisẹ, alasẹ ileeẹsẹ ati awọn adari ẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Kwara sọrọ lati mọ ohun to sokunfa iwọde naa.

Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?
FRSC ṣalaye pe ọkọ Toyota kan ti nọmba rẹ jẹ GGE722KJ gbe okiti ni ẹẹmẹta ko to di pe o jabọ lati ori afara to wa.

Àlàyé rèé lórí ohun táwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ṣe tí ìjọba àpapọ̀ ṣe fọnmú mọ́ wọn lọ́wọ́
Ijọba ti gbe awon igbesẹ to laami-laaka fun atunṣe ikansira ẹni gẹgẹ bi Minisita eto ikansira ẹni ṣe sọ.

"Eko Bridge yóò wà ní títìpa fún àtúnṣe láti ọjọ́ Ìṣẹ́gun" -Ìjọba Eko
Eredi titipa naa bi wọn wi ni fun atunṣe, aabo ati iwadii

Èèyàn mẹ́ta tí ẹ̀yà ara pè níjà bọ́ sọ́wọ́ NDLEA fún ẹ̀sùn òògùn olóró
Femi Babafemi ti i ṣe Adari ikede ni NDLEA, ṣalaye ninu atẹjade naa pe baba agba ẹni ọgọta ọdun (60), torukọ rẹ n jẹ Romanus Nwabara, wa lara awọn akanda ẹda ti ọwọ ba fun ẹsun naa.

Ọkọ ojú omi tí wọ́n ti ṣàwárí ààrùn hantavirus balẹ̀ sí Spain, àyẹ̀wò bẹ̀rẹ̀ fáwọn èrò
Minisita feto ilera Spain, Mónica Gracía sọ pe bí wọn ṣe n ko awọn eeyan bọlẹ ninu ọkọ naa lo n lọ ni mẹsọmẹsọ amọ gbogbo awọn eeyan to wa ninu ọkọ oju omi MS Hondius ni ko ṣoju pe ohunkohun n ṣe wọn.

Lateef Adedimeji, Oboz, àtàwọn òṣèré míì tó gbàmì ẹ̀yẹ ní AMVCA 2026
Ni alẹ ọjọ Abamẹta, ọjọ Kẹsan-an, oṣu Karun-un ni ayẹyẹ naa, to jẹ ikejila iru rẹ waye ni ipinlẹ Eko nibi ti ọpọ awọn agbjumọ oṣere tiata kaakiri ilẹ Africa pejupese si.

EFCC kéde wíwá Sadiya Farouq, mínísítà tẹ́lẹ̀ fún ètò ìbojú-àánú wo aráàlú
Awọn ẹsun bii kiko owo ilu si apo ara ẹni, aṣilo ipo ati igbimọ pọ huwa ọdaran ni EFCC kede pe oun n wa Sadiya Farouq fun.

Ẹgbẹ́ NDC kéde ipò ààrẹ sí Gúúsù Naijiria ní 2027, 2031 fún Àríwá
Ikede yii waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹsan-an oṣu Karun-un ọdun 2026, nibi ipade apapọ ẹgbẹ NDC to waye niluu Abuja.

Kí ló dé tí ọ̀pọ̀ àwọn tó ń bá Gómìnà Seyi Makinde ṣiṣẹ́ níjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń kọ̀wé fipò sílẹ̀?
‎Ohun ti ọpọ awọn to ti kọwe fipo silẹ sọ ni wi pe ija to wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP yoo ṣe idiwo fun awọn ninu eyo idibo to n bọ.

Lateef Adedimeji kéde orúkọ àwọn ìbẹ́ta rẹ àti ọjọ́ tí wẹ̀jẹwẹ̀mu ìdúpẹ́ yóò wáyé
Lateef Adedimeji ni aworan awọn ọmọ kan tawọn kan n gbe kaakiri ori ayelujara ti wọn n pe ni ọmọ oun kii ṣe ọmọ oun o, bi asiko ba to oun ati iyawo oun yoo fi fọto awọn ọmọ naa sita.

Ta ni Stanley Osifo tó fẹ́ kojú Tinubu níbi ètò ìdìbò abẹ́nú APC?
Bayii ọkunrin kan ti jade, to si ti ra fọọmu lati dije tako Tinubu nibi eto idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC to n bọ nibi ti wọn ti maa yan awọn to gbe asia ẹgbẹ oṣelu naa nibi eto idibo gbogbogbo ọdun 2027.

Amotekun nawọ́ gán afurasí agbéṣùmọ̀mí ní ìpínlẹ̀ Ondo
Adeleye sọ pe ọwọ tẹ awọn afurasi naa lasiko tawọn Amotekun ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo mii latari italolobo kan ti wọn gbọ.

Local Housing

This is one of the main issues facing local people. The inadequacy of social housing stock continues to be the main concerns of local people. And it is getting worst.

Read More

Drugs And Illegal Substances

Taking illegal drug is always fraught with danger. You don't need me to tell you that - your grand mother will say the same. The high very often tend to perpetual low that you will never get out from. Get advise now before it is too late

Read More

Knife Attacks

Who goes around with a knive as weapon of protection is deluded. It will inevitably be your comeuppance. Just in case you do not understand, it will kill you. There is no justification for carrying a knive excerpt when you are foraging in the jungle.

Read More

Gang Culture

We were all young once - doing things adults will frown upon. This was at school or in the play grounds. But as we grew up, people we wanted to associate with start to shrink in numbers as our brain matured correspondingly and as a result doing the right thing. Pick your friends judiciously.

Read More

Local Parks

From a personal experience - the local park is a refuge for meditation,physical exploration and mental rejuvination. Just go for a slow run and see how you feel afterwards. Physical and mentally rewarding. Don't just take my words for it - it is a scientific fact. Please do try it.

Read More

24/7 Support

We are your one stop local solution advocate. Dont't carry all that weight on your own we are here to not only relief some of it, but to help you get back to you again.

Read More
Established since 2000

We Are Ready To Assist